Font Size
Gẹnẹsisi 16:15
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Gẹnẹsisi 16:15
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
15 (A)Hagari sì bí ọmọkùnrin kan fún Abramu, Abramu sì pe orúkọ rẹ̀ ní Iṣmaeli.
Read full chapter
Gẹnẹsisi 21:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Gẹnẹsisi 21:2
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 (A)Sara sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan fún Abrahamu ní ọjọ́ ogbó rẹ̀, ní àkókò náà gan an tí Ọlọ́run ti ṣèlérí fún un.
Read full chapter
Gẹnẹsisi 21:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Gẹnẹsisi 21:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
9 Ṣùgbọ́n Sara rí ọmọ Hagari ará Ejibiti tí ó bí fún Abrahamu tí ó fi ṣe ẹlẹ́yà,
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.