Font Size
2 Kọrinti 4:7
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 Kọrinti 4:7
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
7 Ṣùgbọ́n àwa ní ìṣúra yìí nínú ohun èlò amọ̀, kí ọláńlá agbára náà lè jẹ́ ti Ọlọ́run, kí ó má ṣe ti ọ̀dọ̀ wa wá.
Read full chapter
2 Kọrinti 6:7
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 Kọrinti 6:7
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
7 (A)Nínú ọ̀rọ̀ òtítọ́, nínú agbára Ọlọ́run, nínú ìhámọ́ra òdodo ní apá ọ̀tún àti ní apá òsì.
Read full chapter
1 Kọrinti 12:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
1 Kọrinti 12:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
9 Ó fi ẹ̀bùn ìgbàgbọ́ fún ẹlòmíràn, ẹlòmíràn ló sì fi agbára ìwòsàn fún nípa Ẹ̀mí Mímọ́ kan náà.
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.