Font Size
Matiu 10:32
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Matiu 10:32
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
32 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ mi níwájú ènìyàn, òun náà ni èmi yóò jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú Baba mi ní ọ̀run.
Read full chapter
Luku 12:8
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Luku 12:8
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
8 “Mo sì wí fún yín pẹ̀lú, Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ mi níwájú àwọn ènìyàn. Ọmọ ènìyàn yóò sì jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú àwọn angẹli Ọlọ́run:
Read full chapter
Ìṣe àwọn Aposteli 16:31
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìṣe àwọn Aposteli 16:31
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
31 Wọ́n sì wí fún un pé, “Gbá Jesu Kristi Olúwa gbọ́, a ó sì gbà ọ́ là, ìwọ àti àwọn ará ilé rẹ pẹ̀lú.”
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.